Súrà Az-Zalzala الزلزلة
8 verses · Medina · revelation order 93
بِسْمِ ٱللَّهِ ٱلرَّحْمَٰنِ ٱلرَّحِيمِ إِذَا زُلْزِلَتِ ٱلْأَرْضُ زِلْزَالَهَا
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelNígbà tí wọ́n bá mi ilẹ̀ tìtì ní ìmìtìtì rẹ̀,
See all translations of this verse →
وَأَخْرَجَتِ ٱلْأَرْضُ أَثْقَالَهَا
Yoruba Translation - Abu Rahimah Mikaelàti (nígbà) tí ilẹ̀ bá tú àwọn ẹrù tó wúwo nínú rẹ̀ jáde,
See all translations of this verse →
وَقَالَ ٱلْإِنسَٰنُ مَا لَهَا
Yoruba Translation - Abu Rahimah Mikaelènìyàn yó sì wí pé: “Kí l’ó mú un?”
See all translations of this verse →
يَوْمَئِذٍ تُحَدِّثُ أَخْبَارَهَا
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelNí ọjọ́ yẹn ni (ilẹ̀) yóò sọ̀rọ̀ nípa àwọn ìró rẹ̀ (tí ẹ̀dá gbé orí ilẹ̀ ṣe).
See all translations of this verse →
بِأَنَّ رَبَّكَ أَوْحَىٰ لَهَا
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelNítorí pé dájúdájú Olúwa rẹ l’Ó fún un ní àṣẹ (láti sọ̀rọ̀).
See all translations of this verse →
يَوْمَئِذٍ يَصْدُرُ ٱلنَّاسُ أَشْتَاتًا لِّيُرَوْا۟ أَعْمَٰلَهُمْ
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelNí ọjọ́ yẹn, àwọn ènìyàn yóò máa gba ọ̀nà ọ̀tọ̀ọ̀tọ̀ lọ nítorí kí wọ́n lè fi àwọn iṣẹ́ wọn hàn wọ́n.
See all translations of this verse →
فَمَن يَعْمَلْ مِثْقَالَ ذَرَّةٍ خَيْرًا يَرَهُۥ
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelNítorí náà, ẹni tí ó bá ṣe iṣẹ́ rere ní òdíwọ̀n ọmọ iná-igún, ó máa rí i.
See all translations of this verse →
وَمَن يَعْمَلْ مِثْقَالَ ذَرَّةٍ شَرًّا يَرَهُۥ
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelẸni tí ó bá sì ṣe iṣẹ́ aburú ní òdíwọ̀n ọmọ iná-igún, ó máa rí i.[1]
See all translations of this verse →
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
→