Súrà An-Naas الناس
6 verses · Mecca · revelation order 21
بِسْمِ ٱللَّهِ ٱلرَّحْمَٰنِ ٱلرَّحِيمِ قُلْ أَعُوذُ بِرَبِّ ٱلنَّاسِ
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelSọ pé: “Mo sá di Olúwa àwọn ènìyàn,
See all translations of this verse →
مَلِكِ ٱلنَّاسِ
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelỌba àwọn ènìyàn,
See all translations of this verse →
إِلَٰهِ ٱلنَّاسِ
Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelỌlọ́hun àwọn ènìyàn,[1]
See all translations of this verse →
مِن شَرِّ ٱلْوَسْوَاسِ ٱلْخَنَّاسِ
Yoruba Translation - Abu Rahimah Mikaelníbi aburú (aṣ-Ṣaetọ̄n) oníròyíròyí, olùsásẹ́yìn (fún ẹni tó bá ń dárúkọ Allāhu[1]).
See all translations of this verse →
ٱلَّذِى يُوَسْوِسُ فِى صُدُورِ ٱلنَّاسِ
Yoruba Translation - Abu Rahimah Mikael(aṣ-Ṣaetọ̄n ni) ẹni tí ó ń kó ròyíròyí sínú àwọn ọkàn ènìyàn.
See all translations of this verse →
مِنَ ٱلْجِنَّةِ وَٱلنَّاسِ
Yoruba Translation - Abu Rahimah Mikael(Ṣaetọ̄n náà) wà nínú àwọn àlùjànnú àti àwọn ènìyàn.”
See all translations of this verse →
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
→