caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà An-Naml, ẹsẹ 35

Mecca · revelation order 48 · 27:35

وَإِنِّى مُرْسِلَةٌ إِلَيْهِم بِهَدِيَّةٍ فَنَاظِرَةٌۢ بِمَ يَرْجِعُ ٱلْمُرْسَلُونَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelDájúdájú mo máa fi ẹ̀bùn kan ránṣẹ́ sí wọn. Mo sì máa wo ohun tí àwọn ìránṣẹ́ yóò mú padà (ní èsì).”
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70