caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà Al-Anbiyaa, ẹsẹ 80

Mecca · revelation order 73 · 21:80

وَعَلَّمْنَٰهُ صَنْعَةَ لَبُوسٍ لَّكُمْ لِتُحْصِنَكُم مِّنۢ بَأْسِكُمْ فَهَلْ أَنتُمْ شَٰكِرُونَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelA tún fún un ní ìmọ̀ nípa ṣíṣe ẹ̀wù irin fún yín nítorí kí ó lè jẹ́ odi ìṣọ́ fún yín níbi ogun yín. Nítorí náà, ǹjẹ́ olùdúpẹ́ (fún Allāhu) ni ẹ̀yin bí?
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70