caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà Al-Hijr, ẹsẹ 39

Mecca · revelation order 54 · 15:39

قَالَ رَبِّ بِمَآ أَغْوَيْتَنِى لَأُزَيِّنَنَّ لَهُمْ فِى ٱلْأَرْضِ وَلَأُغْوِيَنَّهُمْ أَجْمَعِينَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelÓ wí pé: “Olúwa mi, fún wí pé O ti ṣe mí ní ẹni anù, dájúdájú emí yóò ṣe (aburú) ní ọ̀ṣọ́ fún wọn lórí ilẹ̀. Dájúdájú èmi yó sì kó gbogbo wọn sínú anù
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70