caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà Al-Ma'aarij, ẹsẹ 14

Mecca · revelation order 79 · 70:14

وَمَن فِى ٱلْأَرْضِ جَمِيعًا ثُمَّ يُنجِيهِ

Yoruba Translation - Abu Rahimah Mikaelàti gbogbo ẹni tó wà lórí ilẹ̀ ayé pátápátá, (ó máa fẹ́ fi wọ́n ṣèràpadà ẹ̀mí ara rẹ̀ níbi Ìyà). Lẹ́yìn náà, (ó máa fẹ́) kí Allāhu gba òun là (nínú ìyà Iná).
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70