caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà An-Nisaa, ẹsẹ 117

Medina · revelation order 92 · 4:117

إِن يَدْعُونَ مِن دُونِهِۦٓ إِلَّآ إِنَٰثًا وَإِن يَدْعُونَ إِلَّا شَيْطَٰنًا مَّرِيدًا

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelWọn kò pe kiní kan lẹ́yìn Allāhu bí kò ṣe àwọn abo òrìṣà.[1] Wọn kò sì pe kiní kan bí kò ṣe ṣaetọ̄n olùyapa.
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70