caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà Adh-Dhaariyat, ẹsẹ 35

Mecca · revelation order 67 · 51:35

فَأَخْرَجْنَا مَن كَانَ فِيهَا مِنَ ٱلْمُؤْمِنِينَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelNítorí náà, A mú àwọn tó jẹ́ onígbàgbọ́ òdodo jáde kúrò nínú (ìlú náà).
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70