caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà An-Naml, ẹsẹ 37

Mecca · revelation order 48 · 27:37

ٱرْجِعْ إِلَيْهِمْ فَلَنَأْتِيَنَّهُم بِجُنُودٍ لَّا قِبَلَ لَهُم بِهَا وَلَنُخْرِجَنَّهُم مِّنْهَآ أَذِلَّةً وَهُمْ صَٰغِرُونَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelPadà sí ọ̀dọ̀ wọn. Dájúdájú à ń bọ̀ wá bá wọn pẹ̀lú àwọn ọmọ ogun tí wọn kò lè kojú rẹ̀. Dájúdájú a máa mú wọn jáde kúrò nínú (ìlú wọn) ní ẹni yẹpẹrẹ, tí wọn yó sì di ẹni àbùkù.”
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70