caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà Al-Anbiyaa, ẹsẹ 94

Mecca · revelation order 73 · 21:94

فَمَن يَعْمَلْ مِنَ ٱلصَّٰلِحَٰتِ وَهُوَ مُؤْمِنٌ فَلَا كُفْرَانَ لِسَعْيِهِۦ وَإِنَّا لَهُۥ كَٰتِبُونَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelNítorí náà, ẹnikẹ́ni tí ó bá ṣe nínú àwọn iṣẹ́ rere, tí ó sì jẹ́ onígbàgbọ́ òdodo, kò sí kíkọ̀ fún iṣẹ́ rẹ̀. Àti pé dájúdájú Àwa máa ṣe àkọsílẹ̀ rẹ̀ fún un.
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70