caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà Al-Anbiyaa, ẹsẹ 86

Mecca · revelation order 73 · 21:86

وَأَدْخَلْنَٰهُمْ فِى رَحْمَتِنَآ إِنَّهُم مِّنَ ٱلصَّٰلِحِينَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelA sì fi wọ́n sínú ìkẹ́ Wa. Dájúdájú wọ́n wà nínú àwọn ẹni rere.
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70