caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà Az-Zukhruf, ẹsẹ 87

Mecca · revelation order 63 · 43:87

وَلَئِن سَأَلْتَهُم مَّنْ خَلَقَهُمْ لَيَقُولُنَّ ٱللَّهُ فَأَنَّىٰ يُؤْفَكُونَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelÀti pé tí o bá bi wọ́n léèrè pé: “Ta ni Ó dá wọn?”, dájúdájú wọn á wí pé: “Allāhu ni.” Nítorí náà, báwo ni wọ́n ṣe ń ṣẹ́rí wọn kúrò níbi òdodo?
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70