caseriqÌwádìí ìtumọ̀ nínú Al-Ƙur'ān

Súrà Aal-i-Imraan, ẹsẹ 60

Medina · revelation order 89 · 3:60

ٱلْحَقُّ مِن رَّبِّكَ فَلَا تَكُن مِّنَ ٱلْمُمْتَرِينَ

Yoruba Translation - Abu Rahimah MikaelÒdodo ni láti ọ̀dọ̀ Olúwa rẹ. Nítorí náà, má ṣe wà nínú àwọn oníyèméjì.
Looking for a topic? Try the meaning search — your question is scanned across all 6,236 verses.
Èdè — 70